D.O. Fagunwa
Born
Oke-Igbo, Nigeria
Died
December 09, 1963
Genre
|
Ògbójú Ọdẹ nínú Igbó Irúnmọlẹ̀
—
published
1938
—
11 editions
|
|
|
Ìrìnkèrindò Nínú Igbó Elégbèje
—
published
1940
—
2 editions
|
|
|
Ìrèké-Oníbùdó
—
published
1949
|
|
|
The Forest of God
—
published
1946
—
2 editions
|
|
|
Àdììtú Olódùmarè
—
published
1963
|
|
|
400 İlah Ormanı
by |
|
“ELÉYÌÍ NI ÀÀFIN ÀRÒGÌDÌGBÀ TÍ Í SE OLÓRÍ ẸJA INÚ OMI, ỌDÚN ÀRỌ̀GÌDÌGBÀ SÚNMÓ ETÍLÉ KÍ ÀWỌN EBỌRA ÌSÀLÈ IBÚ OMI ÒKUN LỌ MÁA WÁ ÀWỌN ỌMỌ ÈNÌYÀN WÁ KÍ WÓN FI SE ÀRÍYÁ ỌDÚN ỌBA'.”
― Ìrèké-Oníbùdó
― Ìrèké-Oníbùdó
“Arogidigba ni eyini. Ko tile jo eja rara, ó dabi
omobinrin ó sì di irun ori rẹ̀ winnikin ó da asọ àrán tí àwò rẹ̀ dàbí aṣo aláró tí wón sèsè rẹ bora, wón sì fi àrán pupa bo ẹ̀gbé ogiri léyìn rẹ̀, àtègùn kéékèèkéé kan báyìí ni wón fi òkúta se láti ìsàlẹ̀ lọ dé òkè ibi tí Àrògidigbà wà, gbogbo àyíká ibẹ̀ sì ní ẹwà gidigidi.
"Nígbà tí ó rí wa ó dide, igbà tí ó sì dide yìí ni mo tóó wáá rí i pé irù wà ní idi rè bii ti ẹja.”
― Ìrèké-Oníbùdó
omobinrin ó sì di irun ori rẹ̀ winnikin ó da asọ àrán tí àwò rẹ̀ dàbí aṣo aláró tí wón sèsè rẹ bora, wón sì fi àrán pupa bo ẹ̀gbé ogiri léyìn rẹ̀, àtègùn kéékèèkéé kan báyìí ni wón fi òkúta se láti ìsàlẹ̀ lọ dé òkè ibi tí Àrògidigbà wà, gbogbo àyíká ibẹ̀ sì ní ẹwà gidigidi.
"Nígbà tí ó rí wa ó dide, igbà tí ó sì dide yìí ni mo tóó wáá rí i pé irù wà ní idi rè bii ti ẹja.”
― Ìrèké-Oníbùdó
Topics Mentioning This Author
| topics | posts | views | last activity | |
|---|---|---|---|---|
| Around the World ...: Stacia's 2022 Translated Language Challenge | 2 | 46 | Dec 31, 2022 10:25PM | |
| Catching up on Cl...: Erin’s 2025 Breakfast Buffet | 10 | 38 | Dec 08, 2024 09:13AM | |
| Catching up on Cl...: April 2025 Reading Plans | 20 | 51 | Apr 30, 2025 11:44AM | |
| Great African Reads: Erin’s 2025 African Reads Challenge | 4 | 23 | Jun 20, 2025 05:53AM | |
| Catching up on Cl...: Erin’s 2025 Bingo Challenge | 35 | 58 | Dec 30, 2025 07:43AM |

















